Taiwo Olubunmi Abioye jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n nínú ìmọ̀ Englisi ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Òun ni obìnrin àkọ́kọ́ láti di Ìgbàkejì adarí Covenant University.[1]

Taiwo Abioye
Ọ̀jọ̀gbọ́n nínú ìmò Englisi ní Covenant University
In office
2013–2016
Ígbákejì adarí at Covenant University
In office
2012–2016
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí17 Oṣù Kínní 1958 (1958-01-17) (ọmọ ọdún 66)
Ipinle Kaduna
ResidenceCanaanland, Ipinle Ogun
Alma materAhmadu Bello University
(Bachelor of Education in Language Arts)
Ahmadu Bello University
( Master of Arts in English)
Ahmadu Bello University
(Doctor of Philosophy in English)

Ìpìlẹ̀ àti Ẹ̀kọ́ rẹ̀ àtúnṣe

A bí Taiwo ní ọjọ́ Kẹtàdínlọ́gún oṣù kínní ọdun 1958, ní Kaduna sínú ìdílé àwọn òbí tó wá láti Ìpínlẹ̀ Ogun, Abioye gba àmì-ẹ̀yẹ àkọ́kọ́ nínú ìmò Language Arts Yunifásítì Àmọ́dù Béllò. Bákan náà ẹ̀wẹ̀, ó tẹ̀síwájú láti gba àmì-ẹ̀yẹ Master àti ti Dókítá ní ilé-ìwé kan náà ní ọdun 1992 àti 2004.[2] Ní ọdun 1982, Abioye gba àmì-ẹ̀yẹ akẹ́kọ̀ọ́ tó mọ̀wé jùlọ ni ẹ̀ka Inglisi ti Yunifásitì Àmọ́dù Béllò.[3]

Àwọn Ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. "Oyedepo urges FG to Increase funding to education". World Stage. January 18, 2018. Archived from the original on 2018-01-30. Retrieved 2018-01-30. 
  2. admin (2017-11-22). "Taiwo Abioye" (PDF). covenantuniversity.edu.ng. Retrieved 2017-11-22. [Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
  3. admin. "Prof Taiwo Olubunmi Abioye". covenantuniversity.edu.ng. Archived from the original on 2017-09-24. Retrieved 2017-11-23.