Tope Adenibuyan tí ọ̀pọ̀ ènìyàn mọ̀ sí Teddy A jẹ́ olórin tàkasúfèé, òṣèrẹ́kùnrin àti olùkọ orin sílẹ̀ ní orílè-èdè Nàìjíríà. Ó gbajúmọ̀ fún ìkópa rẹ̀ nínú fíìmù Foreigner's God.[1][2]

Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé àti ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀

àtúnṣe

Wọ́n bi sí ìlú Èkó, ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kí ó tó kó lọ sí America níbi tí ó ti gboyè ẹ̀kọ́ ní University of Texas.

Ìgbésí ayé ara ẹni

àtúnṣe

Teddy A fẹ́ akẹgbẹ́ rẹ̀ tí wọ́n jìjọ wà nínú ètò Big Brother Naija, ìyẹn Bamike Olawunmi, wọ́n sì jọ bí ọmọ méjì pọ̀, àmọ́ Teddy A ní ọmọkùnrin kan, láti ọ̀dọ̀ obìnrin mìíràn.[3][4][5]

Iṣẹ́ orin kíkọ

àtúnṣe

Teddy A bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ orin kíkọ ní America, bẹ́ẹ̀ sì ni ó ti kọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ orin tí ó sì ti ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn olórin mìíràn bí i Timaya, P-Square, Wizkid, àti Flavour.

Àwọn ìtọ́kasí

àtúnṣe
  1. "Teddy A: I am all for music, acting, business". The Guardian Nigeria News – Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 8 January 2022. Retrieved 2022-07-26. 
  2. Nwogu, Precious 'Mamazeus' (10 May 2022). "Ifan Michael's 'Foreigner's God' acquired by Amazon Prime". Pulse Nigeria. Retrieved 2022-07-26. 
  3. Augoye, Jayne (16 November 2019). "BBNaija's Teddy A, Bam Bam wed in Dubai". Premium Times Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-07-26. 
  4. Daniels, Ajiri (8 September 2019). "Fans excited as Teddy A, BamBam wed". The Sun Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-07-26. 
  5. "BamBam & Teddy A Expecting Second Child". The Guardian Nigeria News – Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 9 February 2022. Archived from the original on 2022-03-08. Retrieved 2022-07-26.