Toyin Bolaji Adegoke tí a bí ní ọjọ́ kẹrìnlélógún, osù Ògún, ọdún 1964 jẹ́ adájọ́ ilé-ẹjọ́ ìjọba àpapọ̀ ti orílẹ̀-èdẹ̀ Nàìjíríà[1]. Ìlú Ìbàdànìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ní wọ́n bí í sí.

Èkọ́. àtúnṣe

Ó ka ìwé mẹ́wàá rẹ̀ tán ní Ojuku Grammar School ní ọdún ní ọdún 1981[2]. Ó tẹ̀síwájú nínú ẹ̀kọ́ rẹ̀ ní fásítì Maiduguri, ní ìpínlẹ̀ Maiduguri lọ́dún 1987 láti kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú ìmọ̀ èdè Gẹ̀ẹ́sì (English).

Àwọn ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. "::::: Hon.Justice Toyin Bolaji Adegoke , Federal High Court Nigeria :::::". ::::: Welcome to the Official Website of Federal High Court Nigeria :::::. Retrieved 2023-03-11. 
  2. "Toyin Bolaji Adegoke". Wikidata. 1964-08-24. Retrieved 2023-03-11.