Yemisi Edun ni adari àgbà ile ifowopamosi ti First City Monument Bank(FCMB), òun ni obinrin akoko ti o di ipò náà mú. A yàn sípò náà ní 13 July 2021 léyìn ìgbà tí Adam Nuhu fi ipo náà sílè nitori èsùn biba ìyàwó elomiran sun tí a fi kan.[1] Yemisi jé omobibi ìpínlè Èkó.

Yemisi Edun
Ádárì àgbà First City Monument Bank
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
13 July 2021
AsíwájúAdam Nuhu
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Education
ProfessionBanker

Èkó rè àtúnṣe

Yemisi Edun gba àmì-èye Bachelor's Degree nínú imo Chemistry ní Yunifásitì ti ilé ìfé. O tún tèsíwájú ní yunifásitì ti Liverpool, níbi ti ó ti gba master's degree ní International accounting and finance.[2]

Isé rè àtúnṣe

O bèrè ise gégé bi onibojuto owo ilé-isé Akintola Williams and Co. ni odun 1987, o padà di alakoso agba ilé-isé náà koto dipe ó darapo mó ilé ifowopamosi tí FCMB ní odun 2000. Ó jé adari àgbà ní èka owó koto dipe wón yan sípò adari àgbà gbogbo ilé ifowopamosi náà.

Àwon ìtókasí àtúnṣe

  1. Adamolekun, Ronald (2021-07-13). "FCMB appoints Yemisi Edun to replace Adam Nuru as CEO". Premium Times Nigeria. Retrieved 2022-05-28. 
  2. "Mrs. Yemisi Edun - Managing Director". First City Monument Bank. Retrieved 2022-05-28.