Yetunde Onanuga (tí a bí ní 11 September 1960) jé òtòkùlú olósèlú ní Naijiria àti ígbákejì Gomina ipinle Ògùn teleri.[1]

Yetunde Onanuga
Deputy Governor of Ogun State
In office
2015–2019
GómìnàIbikunle Amosun
AsíwájúSegun Adesegun
Arọ́pòNoimot Salako-Oyedele
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí11 Oṣù Kẹ̀sán 1960 (1960-09-11) (ọmọ ọdún 63)
Ibadan, British Nigeria
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAll Progressives Congress (APC)

Ayé rè àtúnṣe

A bí Onanuga ní ilé iwosan Adeoyo, ìlú Ibadan, olú-ìlú Ìpínlè Oyo, oruko baba rè ni Fabamwo [2] O koko kàwé ní ipinle ogun ko to dipe o kawe ni ìlú Eko nibi to ti gba owe eri fún isé olukoni. O pada tèsíwájú lati gba àmì-èye MBA ni yunodasoti ipinle Ogun. Oun sise pelu ijoba ipinle eko Lori oro adugbo nígbà tí a yan láti díje pèlú Ibikunle Amosun ni odun 2015. Ígbákejì ibikunle Amosun nígbà sáà àkókò rè ti lp sí egbe oselu míràn, Amosun yan Onanuga larin awon méta.[3] A yan Onanuga sípò ígbákejì Gomina labe egbe oselu APC.

Àwon Ìtókasí àtúnṣe

  1. "Onanuga emerges new Ogun deputy governor". Daily Trust. 2014-12-16. Retrieved 2022-05-30. 
  2. "Onanuga: Round peg in round hole". The Nation Newspaper. 2015-01-07. Retrieved 2022-05-30. 
  3. "How Amosun’s running mate emerged". Vanguard News. 2014-12-18. Retrieved 2022-05-30.