Damilola Sunday Olawuyi
Damilola Sunday Olawuyi, SAN, FCIArb, jẹ́ agbani-nímọ̀ràn káàkiri àgbáyé, ọ̀jọ̀gbọ́n nínú ìmọ̀ òfin, òǹkọ̀wé àti agbaniníyànjú lórí ọ̀rọ̀ epo-rọ̀bì, iná, ìwa-ohun-àlùmọ́nì àti òfin.[1] Òun ni igbá kejì adarí Yunifasiti Afe Babalola, Ado Ekiti, Nigeria . [2] Wọ́n fún ọ̀jọ̀gbọ́n Ọjọgbọn Ọlawuyi ní ìgbéga sí ipò ọ̀jọ̀gbọ́n kíkún nígbà tó wà ní ọmọdún méjìlélọ́gbọ̀n 32. Ó di ọkàn lára àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n tó kéré jù lọ nínú ìtàn ìmọ̀ òfin ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Damilola Sunday Olawuyi | |
---|---|
Lọ́wọ́lọ́wọ́ | |
Ó gun orí àga Oṣù Kẹ̀wá 1, 2019 | |
Àwọn àlàyé onítòhún | |
Ọjọ́ìbí | Damilola Sunday Olawuyi Oṣù Kẹjọ 28, 1983 Ibadan, Oyo State, Nigeria |
Alma mater | |
Occupation |
|
Website | damilolaolawuyi.com |
Ó di alágbàwí àgbà ti orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ìyẹn Senior Advocate of Nigeria ( Queen's Counsel eqv.) ní ọdún 2020, ẹni ọdún mẹ́tàdínlógójì, ó di ọmọ ilé ẹ̀kọ́ àbíkẹ́yìn tí wọ́n gbéga sí ipò àgbà agbẹjọ́rò lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà. [4] [5] [6]
Ó jẹ́ igbá kejì alága tíInternational Law Association . [7] Ó ti ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bíi ti ṣe iranṣẹ bi BOK Visiting International Professor (VIP) ní University of Pennsylvania Law School,
ọ̀jọ̀gbọ́n tó ṣe àbẹwò síColumbia Law School, New York,[9] China University of Political Science àti Law, IAS Vanguard Fellow ní University of Birmingham,[10] àti olùṣèwádìí àgbà ní Oxford Institute fún ẹ̀kọ́ Energy.
Ní ọdún 2019, ó jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n tó ṣe àbẹ̀wò sí Herbert Smith Freehills at Cambridge University.[12] Ó ti ṣe ìdánilẹ́kọ̀ọ́ lórí òfin tó dá lórí ọ̀rọ̀ iná ní orílẹ̀-èdè ogójì. Ní ọdún 2020, wọ́n yàn án gẹ́gẹ́ bíi amòye olómìnira lórí African Union's Working Group lórí àwọn ilé-iṣẹ́ kan, àyíká àti ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn. [13] Ní ọdún 2021, Ààrẹ Muhammadu Buhari yàn án gẹ́gẹ́ bíi ọmọ-ẹgbẹ́ igbìmọ̀ ìṣàkóso ti Nigeria Extractive Industries Transparency Initiative.[14][15] Ní ọdún 2022, ààrẹ United Nations Human Rights Council yàn án láti jẹ́ aṣojú ilẹ̀ Afirika gẹ́gẹ́ bíi Amòye olómìnira lórí ìdókòwò àti ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn. [16] Ó jẹ́ alága UNESCO lórí òfin agbègbè àti Sustainable Development ní Hamad Bin Khalifa University, Doha, Qatar.
Ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀ àtúnṣe
Ó jẹ́ ọmọ ìlú Igbajo ní agbègbè ìjọba ìbílẹ̀ Boluwaduro ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, [18] ìlú Ibadan ní wọ́n bí i sí. Ó gba ẹ̀kọ́ alákòóbẹ̀rẹ̀ rẹ̀ ní INRI Nursery and Primary School, ní Ìbàdàn, ó sì lọ sí Igbinedion Secondary School, Benin City, láti lọ parí ẹ̀kọ́ girama rẹ̀. Ibẹ̀ sì ni ó ti jókòó láti kọ ìdánwò àṣekágbá láti gba ìwé-ẹ̀rí WAEC ní ọdún 2000. Lákòókò tí ó wà ní ilé-ìwé, wọ́n mọ̀ ọ́ sí “Authority” nítorí ìfẹ́ tó ní sí ọ̀rọ̀ ìṣèlú, òfin àti orílẹ̀-èdè. Ó máa ń fi ìtara ka ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìwé-ìròyìn tó gbajúmọ̀ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nígbà náà.
Awards ati iyin àtúnṣe
- 2020: Alagbawi agba ti Nigeria .
Àwọn ìtọ́kasí àtúnṣe
- ↑ "Olawuyi: 'International law emphasizes need for consent of communities that may be affected by activity or project'". Guardian Newspaper. Guardian Newspaper. March 5, 2019.
- ↑ Nigerian Lawyers News (October 12, 2019). "Professor Damilola S Olawuyi appointed as Deputy Vice Chancellor at Afe Babalola University, Ado Ekiti". Nigerian Lawyers News. Nigerian Lawyers News.
- ↑ "PROFILE: Meet Olawuyi, Nigeria's youngest SAN who became a law professor at 32". TheCable (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2020-11-21. Retrieved 2023-03-26.
- ↑ "NBA hails LPPC as Ahonaruogho, Alabi, Olawuyi, 69 others make SAN list". Nation News. 2020. https://thenationonlineng.net/nba-hails-lppc-as-ahonaruogho-alabi-olawuyi-69-others-make-san-list/.
- ↑ "Meet The Youngest Academic To Become A Senior Advocate Of Nigeria". Nigerian Lawyers. November 15, 2020. https://thenigerialawyer.com/meet-the-youngest-academic-to-become-a-senior-advocate-of-nigeria/.
- ↑ "Oyetola Congratulates Prof. Olawuyi, Adesina, Hussein On Their Elevation To SAN". The Gazelle News. November 17, 2020. https://www.thegazellenews.com/2020/11/oyetola-congratulates-prof-olawuyi-adesina-hussein-on-their-elevation-to-san/.
- ↑ "Patrons & Officers". International Law Association. International Law Association. International Law Association. Retrieved October 25, 2019.
- ↑ "Bok VIPs". www.law.upenn.edu (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-12-18.
- ↑ "DR. DAMILOLA OLAWUYI JOINS SABIN CENTER AS VISITING SCHOLAR". Columbia Law School. Sabin Centre for Climate Change Law, Columbia Law School.
- ↑ "IAS Vanguard Fellow 2019". University of Birmingham. Institute for Advanced Studies, University of Birmingham. Retrieved October 30, 2019.
- ↑ "Damilola Olawuyi, Senior Visiting Research Fellow". Oxford Institute for Energy Studies. Oxford Institute for Energy Studies.
- ↑ "HBKU faculty member bags Cambridge fellowship". Qatar Peninsula News. Qatar Peninsula. August 13, 2018.
- ↑ The Nations Newspaper, The Nation Newspaper (September 22, 2020). "Olawuyi Joins AU Working Group". The Nation Newspaper. The Nation Newspaper. https://thenationonlineng.net/olawuyi-joins-au-working-group/.
- ↑ TNL, Newspaper (2021). "Buhari Appoints Olawuyi, 14 Others Into NEITI Board". TNL. TNL (TNL) (7). https://thenigerialawyer.com/buhari-appoints-olawuyi-14-others-into-neiti-board/.
- ↑ Vanguard, Newspaper (July 22, 2021). "Buhari tasks NEITI's new board on accountability of natural resource revenues". Vanguard. Vanguard Newspaper. Retrieved July 23, 2021.
- ↑ "Olawuyi to represent Africa in United Nations Working Group". https://tribuneonlineng.com/olawuyi-to-represent-africa-in-united-nations-working-group/.
- ↑ "HBKU establishes Unesco Chair on environmental law and sustainability". Gulf-Times (in Èdè Árábìkì). May 22, 2022. Retrieved 2022-05-23.
- ↑ Nigerian, Tribune (December 20, 2020). "Igbajo Town Celebrates 37-Year-Old Professor Turned SAN". Nigerian Tribune (122020). https://tribuneonlineng.com/igbajo-town-celebrates-37-year-old-professor-turned-san/.
- ↑ "U.S. Society of International Law honours Nigerian, Olawuyi". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2023-04-04. Retrieved 2023-04-06.
- ↑ Gbenga-Ogundare, Yejide (2023-04-05). "SAN bags prestigious book prize". Tribune Online (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-04-06.
- ↑ "PROFILE: Meet Olawuyi, Nigeria's youngest SAN who became a law professor at 32". TheCable (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2020-11-21. Retrieved 2023-03-26.