Ahmadu Umaru Fintiri

Olóṣèlú
(Àtúnjúwe láti Umaru Fintiri)

Ahmadu Umaru Fintiri (ojoibi October 27, 1967) ni gomina Ipinle Adamawa lowolowo [1] O fi tele je omo ile Igbimo Asofin Ipinle Adamawa, nibi ti won ti yan gege bi Olori Ile Asofin. O di aropo gomina Ipinle Adamawa fun igba die leyin igba ti gomina Murtala Nyako je yiyokuro lori ipo na ni July 2014,[2][3] ko to gbepo na fun Bala James Ngilari leyin to lo osu meta lori ibe.[4]

Umaru Fintiri
Governor of Adamawa State
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
May 29, 2019
AsíwájúBindo Jibrilla
Acting Governor of Adamawa State
In office
July 16, 2014 – October 1, 2014
AsíwájúMurtala Nyako
Arọ́pòBala James Ngilari
Speaker, Adamawa State Assembly
In office
January 2014 – July 16, 2014
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbíOctober 27, 1967
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúPeople's Democratic Party, PDP



Itokasi àtúnṣe

  1. https:punchng.com/breaking-inec-declares-pdps-fintiri-winner-of-adamawa-governorship-election/amp/
  2. Tukur, Sani. "Adamawa Speaker, Umaru Fintiri, sworn in as Acting Governor". Premium Times. Retrieved 15 February 2019. 
  3. Olaotan, Falade. "EXCLUSIVE: Why Adamawa PDP flag bearer, Umaru Fintiri’s name appeared on Buhari’s travel ban list". The News Guru. Retrieved 15 February 2019. 
  4. Musa, Njadvara. "Fintiri, Buni win tickets in Adamawa, Yobe". Guardian. Retrieved 15 February 2019.